Gẹnẹsisi 1:1

Gẹnẹsisi 1:1

  Ni àtètèkóse Olórun dá òrun àti aiyé   English Translation:  “In the beginning God created the heavens and the earth”-Genesis. 1:1 Explanation: This iconic verse from the book of Genesis serves as the opening line of the Bible and the...
Proverbs 3:6

Proverbs 3:6

  In all thy ways acknowledge him, and he shall direct thy paths.   Yoruba Translation: Mọ̀ ọ́n ní gbogbo ọ̀nà rẹ     òun yóò sì máa tọ́ ipa ọ̀nà rẹ.   Explanation: In Proverbs 3:6, the wise king Solomon offers a life-changing principle: when we...
Philippians 4:4

Philippians 4:4

  Rejoice in the Lord always: and again I say, Rejoice.   Yoruba Translation: “Ẹ máa yọ̀ nínú Olúwa nígbà gbogbo: mo sì tún wí pé. Ẹ máa yọ̀”_ Fílípì.4:4   Explanation: This powerful verse from Paul’s letter to the Philippians urges...
Fílípì 4:6

Fílípì 4:6

Ẹ má ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ pẹ̀lú ìdúpẹ́, ẹ máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run. English Translation: “Be careful for nothing; but in every thing by prayer and supplication with thanksgiving let your requests be made...
Isaiah 9:6

Isaiah 9:6

  Nítorí a bí ọmọ kan fún wa,     a fi ọmọkùnrin kan fún wa, ìjọba yóò sì wà ní èjìká rẹ̀.     A ó sì máa pè é ní: Ìyanu Olùdámọ̀ràn, Ọlọ́run Alágbára     Baba ayérayé, Ọmọ ọba aládé Àlàáfíà.   English Translation: “For unto us a child is born, unto us...
Lúùkù 6:38

Lúùkù 6:38

Ẹ fi fún ni, a ó sì fi fún yín; òṣùwọ̀n dáradára, àkìmọ́lẹ̀, àti àmìpọ̀, àkúnwọ́sílẹ̀, ni a ó wọ́n si àyà yín: nítorí òṣùwọ̀n náà tí ẹ̀yin fi wọ́n, òun ni a ó padà fi wọ́n fún yín.   English Translation: “Give, and it shall be given unto you; good measure,...